Òní ni ọjọ́ ìbí Omidan Olawumi Oluwakemisola Olúwa Toyin
Gbogbo akẹ́kọ̀ọ́ ìjìnlẹ̀ èdè ló ń bá ẹ yọ̀ tí wọ́n kí ọ kú oriire òní, wọ́n ní o òní kánjú kú, o òní mọ ìnira láyé rẹ, ọdún èyí yóò jẹ ọ̀tun nínú ayé rẹ nítorí pé
Ọdọọdún là ń rórógbó
Ọdọọdún là ń ráwùsá
Ọdọọdún là ń rọ́mọ obì lórí àtẹ
O ku oriire òní
0 comments:
Post a Comment